Salmos 74

YOR

1 Ọlọ́run, èéṣe tí ìwọ fi kọ̀ wá sílẹ̀ títí láé?

2 Rántí àwọn ènìyàn tí ìwọ ti rà nígbà àtijọ́,

3 Yí ẹsẹ̀ rẹ padà sí ìparun ayérayé wọn,

4 Àwọn ọ̀tá rẹ ń bú ramúramù

5 Wọ́n ń rí bí ọkùnrin tí ó gbé àáké rẹ̀ sókè

6 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, iṣẹ́ ọnà fínfín,

7 Wọ́n sun ibi mímọ́ rẹ lulẹ̀

8 Wọ́n wí ní ọkàn wọn. “Àwa ó run wọ́n pátápátá!”

9 A kò fún wa ní àmì iṣẹ́ ìyanu kankan;

10 Àwọn ọ̀tá yóò ti kùn sí ọ pẹ́ tó, Ọlọ́run?

11 Èéṣe tí ìwọ fi dá ọwọ́ rẹ dúró, ọwọ́ ọ̀tún rẹ?

12 Ṣùgbọ́n ìwọ Ọlọ́run ni ọba mi láti ìgbà pípẹ́;

13 Ìwọ ni ó la òkun sílẹ̀ nípa agbára rẹ;

14 Ìwọ fọ́ orí Lefitani túútúú, o sì fi ṣe oúnjẹ fun àwọn ẹ̀dá tí ń gbé inú ijù

15 Ìwọ ya orísun omi àti ìṣàn omi;

16 Tìrẹ ni ọ̀sán, tìrẹ ni òru pẹ̀lú;

17 Ìwọ pààlà etí ayé;

18 Rántí bí àwọn ọ̀tá ń kẹ́gàn rẹ, Olúwa

19 Má ṣe fi ẹ̀mí àdàbà rẹ fún ẹranko igbó búburú;

20 Bojú wo májẹ̀mú rẹ,

21 Má ṣe jẹ́ kí àwọn aninilára padà sẹ́yìn nínú ìtìjú

22 Dìde, Ọlọ́run, gba ẹjọ́ ara rẹ rò;

23 Má ṣe gbàgbé ohùn àwọn ọ̀tá rẹ,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado