1 Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a kọ orin ayọ̀ sí Olúwa,
2 Ẹ jẹ́ kí a wá sí iwájú rẹ̀ pẹ̀lú ọpẹ́
3 Nítorí Olúwa Ọlọ́run títóbi ni,
4 Ní ọwọ́ rẹ̀ ni ọ̀gbun ilẹ̀ wà,
5 Tirẹ̀ ni Òkun, nítorí òun ni ó dá a
6 Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a foríbalẹ̀ kí a sìn ín,
7 nítorí òun ni Ọlọ́run wa,
8 “Ẹ má ṣe sé ọkàn yín le gẹ́gẹ́ bí ẹ ti ṣe ní Meriba,
9 nígbà tí àwọn baba yín dán mi wò
10 Fún ogójì ọdún ni èmi fi bínú sí ìran náà;
11 Nítorí náà ni mo kéde ìbúra nínú ìbínú mi,