Salmos 91

YOR

1 Ẹni tí ó gbé ibi ìkọ̀kọ̀ Ọ̀gá-ògo

2 Èmi yóò sọ nípa ti Olúwa pé,

3 Nítòótọ́ òun yóò gbà mí nínú

4 Òun yóò fi ìyẹ́ rẹ̀ bò mí,

5 Ìwọ kì yóò bẹ̀rù nítorí ẹ̀rù òru,

6 tàbí fún àjàkálẹ̀-ààrùn tí ń rìn kiri ní òkùnkùn,

7 Ẹgbẹ̀rún (1,000) yóò ṣubú ní ẹ̀gbẹ́ rẹ,

8 Ìwọ yóò máa wò ó pẹ̀lú ojú rẹ

9 Nítorí ìwọ fi Olúwa ṣe ààbò rẹ,

10 Búburú kan ki yóò ṣubú lù ọ́,

11 Nítorí yóò fi àṣẹ fún àwọn angẹli nípa tìrẹ

12 wọn yóò gbé ọ sókè ní ọwọ́ wọn,

13 Ìwọ yóò rìn lórí kìnnìún àti paramọ́lẹ̀;

14 “Nítorí ti ìfẹ́ rẹ sí mi, èmi yóò gbà ọ́;

15 Òun yóò pè mí, èmi yóò sì dá a lóhùn;

16 Pẹ̀lú ẹ̀mí gígùn ni èmi yóò fi tẹ́ ẹ lọ́rùn,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado