1 Ohun rere ni láti máa fi ọpẹ́ fún Olúwa
2 láti kéde ìfẹ́ rẹ̀ ní òwúrọ̀
3 lára ohùn èlò orin olókùn mẹ́wàá
4 Nítorí ìwọ ni ó mú inú mi dùn
5 Báwo ni iṣẹ́ rẹ tí tóbi tó, Olúwa?
6 Òpè ènìyàn kò mọ̀ ọ́n,
7 nígbà tí àwọn ènìyàn búburú bá rú jáde bí i koríko
8 Ṣùgbọ́n ìwọ Olúwa ni a ó gbéga títí láé.
9 Nítorí nítòótọ́ àwọn ọ̀tá rẹ,
10 Ìwọ ti gbé ìwo mi ga bí i ti màlúù igbó;
11 Ojú mi ti rí ìṣubú àwọn ọ̀tá mi;
12 Olódodo yóò gbèrú bí i igi ọ̀pẹ,
13 tí a gbìn sí ilé Olúwa,
14 Wọn yóò máa so èso ní ìgbà ogbó,
15 láti fihàn pé, “Ẹni ìdúró ṣinṣin ni Olúwa;