Salmos 90

YOR

1 Olúwa, ìwọ ti jẹ́ ibùgbé wa ní gbogbo ìran dé ìran.

2 Kí a tó bí àwọn òkè ńlá

3 Ìwọ yí ènìyàn padà sí erùpẹ̀,

4 Nítorí pé ìgbà tí ẹgbẹ̀rún (1,000) ọdún bá kọjá lójú rẹ,

5 Ìwọ gbá ènìyàn dànù nínú oorun ikú;

6 Lóòtítọ́, ní òwúrọ̀, ó yọ tuntun

7 A pa wá run nípa ìbínú rẹ

8 Ìwọ ti gbé ẹ̀ṣẹ̀ wa ka iwájú rẹ,

9 Gbogbo ọjọ́ wa ń kọjá lọ lábẹ́ ìbínú rẹ;

10 Àádọ́rin ọdún ni iye ọjọ́ ọdún wá,

11 Ta ni ó mọ agbára ìbínú rẹ?

12 Kọ́ wa bí a ti ń kaye ọjọ́ wa dáradára,

13 Yípadà, Olúwa! Yóò ti pẹ́ tó?

14 Tẹ́ wa lọ́rùn ní òwúrọ̀ nínú ìṣeun ìfẹ́ rẹ,

15 Mú inú wa dùn bí ọjọ́ tí ìwọ ti pọ́n wa lójú,

16 Jẹ́ kí a fi iṣẹ́ rẹ̀ han àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀,

17 Jẹ́ kí ẹwà Olúwa Ọlọ́run wa wà lára wa;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado