Salmos 83

YOR

1 Ọlọ́run, má ṣe dákẹ́;

2 Wo bí àwọn ọ̀tá rẹ ti ń rọ́kẹ̀kẹ̀ lọ,

3 Pẹ̀lú àrékérekè ni wọn dìtẹ̀ sí àwọn ènìyàn rẹ;

4 Wọn wí pé, “wá, ẹ jẹ́ kí á pa wọ́n run bí orílẹ̀-èdè,

5 Wọ́n gbìmọ̀ pọ̀ pẹ̀lú ọkàn kan;

6 Àgọ́ Edomu àti ti àwọn ará Iṣmaeli,

7 Gebali, Ammoni àti Amaleki,

8 Asiria pẹ̀lú ti darapọ̀ mọ́ wọn

9 Ṣe sí wọn bí ìwọ ti ṣe sí Midiani

10 ẹni tí ó ṣègbé ní Endori

11 Ṣe àwọn ọlọ́lá wọn bí Orebu àti Seebu,

12 tí ó wí pé, “Ẹ jẹ́ kí a gbà ní ìní

13 Ìwọ Ọlọ́run, ṣe wọ́n bí ààjà,

14 Bí iná ti í jó igbó,

15 bẹ́ẹ̀ ni kí o fi ẹ̀fúùfù líle rẹ lépa wọn

16 Fi ìtìjú kún ojú wọn,

17 Jẹ́ kí ojú kí ó tì wọ́n, kí wọ́n sì dààmú láéláé

18 jẹ́ kí wọn mọ̀ pé ìwọ, tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Olúwa:

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado