Salmos 80

YOR

1 Gbọ́ tiwa, ìwọ olùṣọ́-àgùntàn Israẹli;

2 níwájú Efraimu, Benjamini àti Manase.

3 Mú wa padà bọ̀ sípò, ìwọ Ọlọ́run;

4 Olúwa Ọlọ́run alágbára,

5 Ìwọ ti fi oúnjẹ bọ́ wọn

6 Ìwọ sọ wá di ẹlẹ́yà fún àwọn aládùúgbò wa,

7 Tún wa yípadà, ìwọ, Ọlọ́run alágbára;

8 Ìwọ mú àjàrà jáde láti Ejibiti;

9 Ìwọ ṣí ààyè sílẹ̀ fún un,

10 A bò àwọn òkè mọ́lẹ̀ òkè pẹ̀lú òjìji rẹ̀,

11 O yọ ẹ̀ka rẹ̀ sínú Òkun,

12 Èéṣe tí ìwọ fi wó odi rẹ̀

13 Ìmàdò láti inú igbó ń bá a jẹ́

14 Yípadà sí wa, àwa ń bẹ̀ ọ́, Ọlọ́run alágbára!

15 gbòǹgbò èyí tí ọwọ́ ọ̀tún rẹ ti gbìn,

16 A gé àjàrà rẹ lulẹ̀, a ti fi iná sun ún;

17 Jẹ́ kí ọwọ́ rẹ kí ó wà lára ọkùnrin tí ó wà ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ,

18 Nígbà náà àwa kí yóò yípadà kúrò lọ́dọ̀ rẹ;

19 Tún wa yípadà, Olúwa Ọlọ́run alágbára;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado