1 Gbọ́ tiwa, ìwọ olùṣọ́-àgùntàn Israẹli;
2 níwájú Efraimu, Benjamini àti Manase.
3 Mú wa padà bọ̀ sípò, ìwọ Ọlọ́run;
4 Olúwa Ọlọ́run alágbára,
5 Ìwọ ti fi oúnjẹ bọ́ wọn
6 Ìwọ sọ wá di ẹlẹ́yà fún àwọn aládùúgbò wa,
7 Tún wa yípadà, ìwọ, Ọlọ́run alágbára;
8 Ìwọ mú àjàrà jáde láti Ejibiti;
9 Ìwọ ṣí ààyè sílẹ̀ fún un,
10 A bò àwọn òkè mọ́lẹ̀ òkè pẹ̀lú òjìji rẹ̀,
11 O yọ ẹ̀ka rẹ̀ sínú Òkun,
12 Èéṣe tí ìwọ fi wó odi rẹ̀
13 Ìmàdò láti inú igbó ń bá a jẹ́
14 Yípadà sí wa, àwa ń bẹ̀ ọ́, Ọlọ́run alágbára!
15 gbòǹgbò èyí tí ọwọ́ ọ̀tún rẹ ti gbìn,
16 A gé àjàrà rẹ lulẹ̀, a ti fi iná sun ún;
17 Jẹ́ kí ọwọ́ rẹ kí ó wà lára ọkùnrin tí ó wà ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ,
18 Nígbà náà àwa kí yóò yípadà kúrò lọ́dọ̀ rẹ;
19 Tún wa yípadà, Olúwa Ọlọ́run alágbára;