1 Ọlọ́run, àwọn orílẹ̀-èdè ti wá ilẹ̀ ìní rẹ;
2 Wọn ti fi ara òkú àwọn ìránṣẹ́ rẹ
3 Wọ́n tu ẹ̀jẹ̀ jáde gẹ́gẹ́ bí omi
4 Àwa di ohun ẹ̀gàn sí àwọn tí ó yí wa ká,
5 Nígbà wo, Olúwa? Ní ìwọ ó máa bínú títí láé?
6 Tú ìbínú rẹ jáde sí orílẹ̀-èdè
7 nítorí wọ́n ti run Jakọbu
8 Má ṣe ka ẹ̀ṣẹ̀ àwọn baba wa sí wa lọ́rùn
9 Ràn wá lọ́wọ́, Ọlọ́run Olùgbàlà wa,
10 Àwọn orílẹ̀-èdè yóò máa wí pé,
11 Jẹ́ kí ìmí ẹ̀dùn oǹdè náà wá síwájú rẹ,
12 San án padà sí àyà àwọn aládùúgbò wa nígbà méje
13 Nígbà náà àwa ènìyàn rẹ,