Salmos 76

YOR

1 Ní Juda ni a mọ Ọlọ́run;

2 Àgọ́ rẹ̀ wà ní Salẹmu,

3 Níbẹ̀ ni ó ṣẹ́ ọfà,

4 Ìwọ ni ògo àti ọlá,

5 A kó àwọn alágídí ọkàn ní ìkógun

6 Ní ìfibú rẹ, Ọlọ́run Jakọbu,

7 Ìwọ nìkan ni ó yẹ kí a bẹ̀rù.

8 Ìwọ ń ṣe ìdájọ́ láti ọ̀run,

9 nígbà tí, ìwọ Ọlọ́run,

10 Lóòótọ́, ìbínú rẹ sí àwọn ènìyàn ń mú ìyìn wá fún ọ,

11 Jẹ́ ẹ̀jẹ́ sí Olúwa Ọlọ́run rẹ kí o sì mú un ṣẹ;

12 Ó ké ẹ̀mí àwọn aládé kúrò;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado