1 Ní Juda ni a mọ Ọlọ́run;
2 Àgọ́ rẹ̀ wà ní Salẹmu,
3 Níbẹ̀ ni ó ṣẹ́ ọfà,
4 Ìwọ ni ògo àti ọlá,
5 A kó àwọn alágídí ọkàn ní ìkógun
6 Ní ìfibú rẹ, Ọlọ́run Jakọbu,
7 Ìwọ nìkan ni ó yẹ kí a bẹ̀rù.
8 Ìwọ ń ṣe ìdájọ́ láti ọ̀run,
9 nígbà tí, ìwọ Ọlọ́run,
10 Lóòótọ́, ìbínú rẹ sí àwọn ènìyàn ń mú ìyìn wá fún ọ,
11 Jẹ́ ẹ̀jẹ́ sí Olúwa Ọlọ́run rẹ kí o sì mú un ṣẹ;
12 Ó ké ẹ̀mí àwọn aládé kúrò;