Salmos 69

YOR

1 Gbà mí, Ọlọ́run,

2 Mo ń rì nínú irà jíjìn,

3 Agara dá mi, mo ń pè fún ìrànlọ́wọ́;

4 Àwọn tí ó kórìíra mi láìnídìí

5 Ìwọ mọ òmùgọ̀ mi, Ọlọ́run;

6 Má ṣe dójútì àwọn tí ó ní ìrètí nínú rẹ nítorí mi,

7 Nítorí rẹ ni mo ń ru ẹ̀gàn,

8 Mo jẹ́ àjèjì si àwọn arákùnrin mi;

9 nítorí ìtara ilé rẹ jẹ mí run,

10 Nígbà tí mo sọkún

11 nígbà tí mo wọ aṣọ àkísà,

12 Àwọn tí ó jókòó ní ẹnu ibodè ń bú mi,

13 Ṣùgbọ́n bí ó ṣe ti èmi ni

14 Gbà mí kúrò nínú ẹrẹ̀,

15 Má ṣe jẹ́ kí ìkún omi bò mí mọ́lẹ̀

16 Dá mí lóhùn, Olúwa, nínú ìṣeun ìfẹ́ rẹ;

17 Má ṣe pa ojú rẹ mọ́ fún ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ:

18 Súnmọ́ tòsí kí o sì gbà mí là;

19 Ìwọ ti mọ ẹ̀gàn mi, ìtìjú mi àti àìlọ́lá;

20 Ẹ̀gàn ba ọkàn mi jẹ́,

21 Wọ́n fi òróró fún mi pẹ̀lú ohun jíjẹ mi,

22 Jẹ́ kí tábìlì wọn kí ó di ìkẹ́kùn

23 Kí ojú wọn kì í ó ṣókùnkùn, kí wọn má ṣe ríran,

24 Tú ìbínú rẹ jáde sí wọn;

25 Kí ibùjókòó wọn di ahoro;

26 Nítorí wọ́n ń ṣe inúnibíni sí ẹni tí ìwọ ti lù,

27 Fi ẹ̀sùn kún ẹ̀sùn wọn;

28 Jẹ́ kí a yọ wọ́n kúrò nínú ìwé ìyè

29 Ṣùgbọ́n tálákà àti ẹni-ìkáàánú ni èmí,

30 Èmi yóò fi orin gbé orúkọ Ọlọ́run ga

31 Eléyìí tẹ́ Olúwa lọ́rùn ju ọ̀dá màlúù lọ

32 Àwọn òtòṣì yóò rí, wọn yóò sì yọ̀:

33 Olúwa, gbọ́ ti aláìní,

34 Kí ọ̀run àti ayé yìn ín,

35 nítorí tí Ọlọ́run yóò gba Sioni là

36 àwọn ọmọ ọmọ ọ̀dọ̀ ni yóò máa jogún rẹ̀,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado