Salmos 68

YOR

1 Kí Ọlọ́run kí ó dìde, kí àwọn ọ̀tá rẹ̀ kí ó fọ́nká;

2 Bí ìjì ti ń fẹ́ èéfín lọ,

3 Ṣùgbọ́n kí inú olódodo kí ó dùn

4 Ẹ kọrin sí Ọlọ́run,

5 Baba àwọn aláìní baba àti onídàájọ́ àwọn opó ni Ọlọ́run ní ibùgbé

6 Ọlọ́run gbé aláìlera

7 Nígbà tí ìwọ bá jáde lónìí níwájú àwọn ènìyàn rẹ, Ọlọ́run,

8 Ilẹ̀ mì títí,

9 Ìwọ fún wa ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ òjò, Ọlọ́run;

10 Àwọn ènìyàn rẹ tẹ̀dó síbẹ̀

11 Olúwa ti pàṣẹ ọ̀rọ̀,

12 “Àwọn ọba àti àwọn ológun yára sálọ;

13 Nígbà tí ẹ̀yin dùbúlẹ̀ láàrín agbo ẹran,

14 Nígbà tí Olódùmarè fọ́n àwọn ọba ká ní ilẹ̀ náà,

15 Òkè Baṣani jẹ́ òkè Ọlọ́run;

16 Kí ló dé tí ẹ̀yin fi ń ṣe ìlara,

17 Ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ni kẹ̀kẹ́ ogun Ọlọ́run

18 Ìwọ ti gòkè sí ibi gíga

19 Olùbùkún ni Olúwa,

20 Ọlọ́run wa jẹ́ Ọlọ́run tó ń gbàlà

21 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run yóò tẹ orí àwọn ọ̀tá rẹ̀,

22 Olúwa wí pé, “Èmi ó mú wọn wá láti Baṣani;

23 kí ẹsẹ̀ rẹ kí ó le pọ́n ní inú ẹ̀jẹ̀ àwọn ọ̀tá rẹ,

24 Wọ́n ti rí ìrìn rẹ, Ọlọ́run,

25 Àwọn akọrin wà ní iwájú, àwọn olórin wà lẹ́yìn;

26 Ẹ fi ìyìn fún Olúwa ní ẹgbẹgbẹ́;

27 Níbẹ̀ ní ẹ̀yà kékeré Benjamini wà, tí ó ń darí wọn,

28 Pàṣẹ agbára rẹ, Ọlọ́run;

29 Nítorí tẹmpili rẹ ni Jerusalẹmu

30 Bá àwọn ẹranko búburú wí,

31 Àwọn ọmọ-aládé yóò wá láti Ejibiti;

32 Kọrin sí Ọlọ́run, ẹ̀yin ìjọba ayé,

33 Sí ẹni tí ń gun ọ̀run dé ọ̀run àtijọ́ lókè,

34 Kéde agbára Ọlọ́run,

35 Ìwọ ní ẹ̀rù, Ọlọ́run, ní ibi mímọ́ rẹ;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado