1 Kí Ọlọ́run kí ó dìde, kí àwọn ọ̀tá rẹ̀ kí ó fọ́nká;
2 Bí ìjì ti ń fẹ́ èéfín lọ,
3 Ṣùgbọ́n kí inú olódodo kí ó dùn
4 Ẹ kọrin sí Ọlọ́run,
5 Baba àwọn aláìní baba àti onídàájọ́ àwọn opó ni Ọlọ́run ní ibùgbé
6 Ọlọ́run gbé aláìlera
7 Nígbà tí ìwọ bá jáde lónìí níwájú àwọn ènìyàn rẹ, Ọlọ́run,
8 Ilẹ̀ mì títí,
9 Ìwọ fún wa ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ òjò, Ọlọ́run;
10 Àwọn ènìyàn rẹ tẹ̀dó síbẹ̀
11 Olúwa ti pàṣẹ ọ̀rọ̀,
12 “Àwọn ọba àti àwọn ológun yára sálọ;
13 Nígbà tí ẹ̀yin dùbúlẹ̀ láàrín agbo ẹran,
14 Nígbà tí Olódùmarè fọ́n àwọn ọba ká ní ilẹ̀ náà,
15 Òkè Baṣani jẹ́ òkè Ọlọ́run;
16 Kí ló dé tí ẹ̀yin fi ń ṣe ìlara,
17 Ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ni kẹ̀kẹ́ ogun Ọlọ́run
18 Ìwọ ti gòkè sí ibi gíga
19 Olùbùkún ni Olúwa,
20 Ọlọ́run wa jẹ́ Ọlọ́run tó ń gbàlà
21 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run yóò tẹ orí àwọn ọ̀tá rẹ̀,
22 Olúwa wí pé, “Èmi ó mú wọn wá láti Baṣani;
23 kí ẹsẹ̀ rẹ kí ó le pọ́n ní inú ẹ̀jẹ̀ àwọn ọ̀tá rẹ,
24 Wọ́n ti rí ìrìn rẹ, Ọlọ́run,
25 Àwọn akọrin wà ní iwájú, àwọn olórin wà lẹ́yìn;
26 Ẹ fi ìyìn fún Olúwa ní ẹgbẹgbẹ́;
27 Níbẹ̀ ní ẹ̀yà kékeré Benjamini wà, tí ó ń darí wọn,
28 Pàṣẹ agbára rẹ, Ọlọ́run;
29 Nítorí tẹmpili rẹ ni Jerusalẹmu
30 Bá àwọn ẹranko búburú wí,
31 Àwọn ọmọ-aládé yóò wá láti Ejibiti;
32 Kọrin sí Ọlọ́run, ẹ̀yin ìjọba ayé,
33 Sí ẹni tí ń gun ọ̀run dé ọ̀run àtijọ́ lókè,
34 Kéde agbára Ọlọ́run,
35 Ìwọ ní ẹ̀rù, Ọlọ́run, ní ibi mímọ́ rẹ;