Salmos 67

YOR

1 Kí Ọlọ́run kí ó ṣàánú fún wa kí ó sì bùkún fún wa,

2 kí ọ̀nà rẹ le di mí mọ̀ ní ayé,

3 Kí àwọn ènìyàn kí ó yìn ọ́, Ọlọ́run;

4 Kí orílẹ̀-èdè kí ó yọ̀, kí ó sì kọrin fún ayọ̀,

5 Kí àwọn ènìyàn kí ó yìn ọ́, Ọlọ́run;

6 Nígbà náà ní ilẹ̀ yóò mú ìkórè rẹ̀ wá, Ọlọ́run,

7 Ọlọ́run yóò bùkún fún wa,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado