1 Kí Ọlọ́run kí ó ṣàánú fún wa kí ó sì bùkún fún wa,
2 kí ọ̀nà rẹ le di mí mọ̀ ní ayé,
3 Kí àwọn ènìyàn kí ó yìn ọ́, Ọlọ́run;
4 Kí orílẹ̀-èdè kí ó yọ̀, kí ó sì kọrin fún ayọ̀,
5 Kí àwọn ènìyàn kí ó yìn ọ́, Ọlọ́run;
6 Nígbà náà ní ilẹ̀ yóò mú ìkórè rẹ̀ wá, Ọlọ́run,
7 Ọlọ́run yóò bùkún fún wa,