1 Ẹ hó ìhó ayọ̀ sí Ọlọ́run, ẹ̀yin ilẹ̀ gbogbo!
2 Ẹ kọrin ọlá orúkọ rẹ̀;
3 Ẹ wí fún Ọlọ́run pé, “Ìwọ ti ní ẹ̀rù tó nínú iṣẹ́ rẹ!
4 Gbogbo ayé ń wólẹ̀ fún ọ;
5 Ẹ wá wo ohun tí Ọlọ́run ṣe,
6 Ó yí òkun padà sí ilẹ̀ gbígbẹ,
7 Ó ń jẹ ọba títí láé nípa agbára rẹ̀,
8 Ẹ yin Ọlọ́run wa, ẹ̀yin ènìyàn,
9 Ó ti dá ààbò bo ẹ̀mí wa,
10 Nítorí ìwọ, Ọlọ́run, dán wa wò;
11 Ìwọ mú wa wá sínú ẹ̀wọ̀n
12 Ìwọ mú àwọn ènìyàn gún wá ní orí
13 Èmi ó wá sí tẹmpili rẹ pẹ̀lú ọrẹ ẹbọ sísun,
14 ẹ̀jẹ́ tí ètè mi jẹ́, tí ẹnu mi sì sọ
15 Èmi ó rú ẹbọ sísun ọlọ́ràá sí ọ,
16 Ẹ wá gbọ́ gbogbo ẹ̀yin tí ó bẹ̀rù Ọlọ́run;
17 Mo fi ẹnu mi kígbe sókè sí i,
18 Bí èmi bá gba ẹ̀ṣẹ̀ ní àyà mi,
19 ṣùgbọ́n Ọlọ́run gbọ́ nítòótọ́
20 Ìyìn ni fún Ọlọ́run