1 Ìyìn ń dúró dè ọ́, Ọlọ́run, ní Sioni;
2 Ìwọ tí ó ń gbọ́ àdúrà,
3 Ọ̀ràn àìṣedéédéé borí mi bí ó ṣe ti ìrékọjá wa ni!
4 Ìbùkún ni fún àwọn tí o yàn
5 Ìwọ dá wa lóhùn pẹ̀lú ohun ìyanu ti òdodo,
6 ìwọ tí ó dá òkè nípa agbára rẹ,
7 ẹni tí ó mú rírú omi òkun dákẹ́,
8 Àwọn tí ó ń gbé òkèrè bẹ̀rù,
9 Ìwọ bẹ ayé wò, o sì bomirin;
10 Ìwọ fi bomirin sí aporo rẹ̀
11 Ìwọ fi oore rẹ dé ọdún ní adé,
12 Pápá tútù ní aginjù ń kan
13 Agbo ẹran ni a fi wọ pápá tútù náà ní aṣọ;