Salmos 64

YOR

1 Gbóhùn mi, Ọlọ́run, bí mo ti ń sọ àròyé mi

2 Pa mí mọ́ kúrò lọ́wọ́ ìmọ̀ ìkọ̀kọ̀ àwọn ènìyàn búburú

3 Wọ́n pọ́n ahọ́n wọn bí idà,

4 Wọ́n tafà ní ìkọ̀kọ̀ sí àwọn aláìlẹ́ṣẹ̀:

5 Wọ́n, gba ara wọn níyànjú nínú èrò búburú,

6 Wọ́n gbìmọ̀ àìṣòdodo, wọ́n wí pé,

7 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run yóò ta wọ́n ní ọfà;

8 Ahọ́n wọn yóò sì dojú ìjà kọ wọ́n, yóò sì run wọ́n,

9 Gbogbo ènìyàn yóò máa bẹ̀rù

10 Jẹ́ kí olódodo kí ó yọ̀ nínú Olúwa

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado