1 Ọlọ́run, ìwọ ni Ọlọ́run mi,
2 Èmi ti rí ọ ní ibi mímọ́,
3 Nítorí ìfẹ́ rẹ dára ju ayé lọ,
4 Èmi ó yìn ọ́ níwọ̀n ìgbà tí mo wà láààyè,
5 A ó tẹ́ ọkàn mi lọ́rùn bí ọlọ́ràá oúnjẹ;
6 Nígbà tí mo rántí rẹ lórí ibùsùn mi;
7 Nítorí ìwọ ni ìrànlọ́wọ́ mi,
8 Ọkàn mí fà sí ọ:
9 Àwọn tí ó ń wá ọkàn mí ni a ó parun;
10 Wọn ó ti ọwọ́ idà ṣubú
11 Ṣùgbọ́n ọba yóò yọ̀ nínú Ọlọ́run