1 Nínú Ọlọ́run nìkan ni ọkàn mi ti rí ìsinmi;
2 Òun nìkan ní àpáta mi àti ìgbàlà mi;
3 Ẹ̀yin ó ti máa kọ́lú ènìyàn kan pẹ́ tó?
4 Kìkì èrò wọn ni láti bì ṣubú
5 Nínú Ọlọ́run nìkan ni ìsinmi wà, ìwọ Ọlọ́run mi.
6 Òun nìkan ní àpáta àti ìgbàlà mi;
7 Ìgbàlà mi àti ògo mi dúró nínú Ọlọ́run;
8 Gbẹ́kẹ̀lé ní gbogbo ìgbà, ẹ̀yin ènìyàn;
9 Nítòótọ́, asán ni àwọn ọmọ ènìyàn,
10 Má ṣe gbẹ́kẹ̀lé ìnilára,
11 Ọlọ́run ti sọ̀rọ̀ lẹ́ẹ̀kejì,
12 pẹ̀lúpẹ̀lú, Olúwa, tìrẹ ni àánú;