1 Olúwa, má ṣe bá mi wí nínú ìbínú rẹ
2 Ṣàánú fún mi, Olúwa, nítorí èmi ń kú lọ;
3 Ọkàn mi wà nínú ìrora.
4 Yípadà, Olúwa, kí o sì gbà mí;
5 Ẹnikẹ́ni kò ni rántí rẹ nígbà tí ó bá kú.
6 Agara ìkérora mi dá mi tán.
7 Ojú mi di aláìlera pẹ̀lú ìbànújẹ́;
8 Kúrò lọ́dọ̀ mi, gbogbo ẹ̀yin tí ń ṣe iṣẹ́ ibi,
9 Olúwa ti gbọ́ ẹkún mi fún àánú;
10 Gbogbo àwọn ọ̀tá mi lójú yóò tì, wọn yóò sì dààmú;