Salmos 6

YOR

1 Olúwa, má ṣe bá mi wí nínú ìbínú rẹ

2 Ṣàánú fún mi, Olúwa, nítorí èmi ń kú lọ;

3 Ọkàn mi wà nínú ìrora.

4 Yípadà, Olúwa, kí o sì gbà mí;

5 Ẹnikẹ́ni kò ni rántí rẹ nígbà tí ó bá kú.

6 Agara ìkérora mi dá mi tán.

7 Ojú mi di aláìlera pẹ̀lú ìbànújẹ́;

8 Kúrò lọ́dọ̀ mi, gbogbo ẹ̀yin tí ń ṣe iṣẹ́ ibi,

9 Olúwa ti gbọ́ ẹkún mi fún àánú;

10 Gbogbo àwọn ọ̀tá mi lójú yóò tì, wọn yóò sì dààmú;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado