1 Fi etí sí ọ̀rọ̀ mi, Olúwa,
2 Fi etí sílẹ̀ sí igbe mi fún ìrànlọ́wọ́,
3 Ní òwúrọ̀, Olúwa, ìwọ yóò gbọ́ ohùn mi;
4 Nítorí ìwọ kì í ṣe Ọlọ́run tí ó ní inú dídùn sí búburú;
5 Àwọn agbéraga kò le è dúró
6 ìwọ yóò pa àwọn tí ń ṣe èké run.
7 Ṣùgbọ́n èmi, nípa títóbi àánú rẹ̀,
8 Tọ́ mi, Olúwa, nínú òdodo rẹ,
9 Kò sí ọ̀rọ̀ kan ní ẹnu wọn tí a lè gbàgbọ́;
10 Dá wọn lẹ́bi Ọlọ́run!
11 Ṣùgbọ́n, jẹ́ kí gbogbo àwọn tí ó sádi ọ́ kí ó yọ̀;
12 Dájúdájú, Olúwa, ìwọ bùkún olódodo;