1 Dá mi lóhùn nígbà tí mo bá pè ọ́,
2 Báwo ni yóò ṣe pẹ́ tó, ẹ̀yin ọmọ ènìyàn, tí ẹ ó ṣe sọ ògo mi di ìtìjú?
3 Ṣùgbọ́n kí ẹ mọ̀ pé, Olúwa ti ya ẹni olódodo sọ́tọ̀ fún ara rẹ̀;
4 Ẹ bínú ẹ má ṣe ṣẹ̀,
5 Ẹ rú ẹbọ òdodo
6 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ló ń béèrè pé, “Ta ni yóò ṣe rere fún wa?”
7 Ìwọ ti fi ayọ̀ púpọ̀ kún ọkàn mi
8 Èmi yóò dùbúlẹ̀, èmi ó sì sùn ní àlàáfíà,