1 Olúwa Ọlọ́run mi, ààbò mi wà nínú rẹ;
2 kí wọn ó má ba à fa ọkàn mi ya gẹ́gẹ́ bí kìnnìún,
3 Olúwa Ọlọ́run mi, tí èmi bá ṣe èyí
4 bí èmi bá ṣe ibi sí ẹni tí ń wá àlàáfíà pẹ̀lú mi,
5 nígbà náà, jẹ́ kí ọ̀tá mi lé mi kí wọn sì mú mi;
6 Dìde, Olúwa, nínú ìbínú rẹ;
7 Kí ìpéjọ àwọn ènìyàn yíká.
8 Jẹ́ kí Olúwa ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn.
9 Ọlọ́run Olódodo,
10 Ààbò mi ń bẹ lọ́dọ̀ Ọlọ́run,
11 Ọlọ́run ni onídàájọ́ òtítọ́,
12 Bí kò bá yípadà,
13 Ó ti pèsè ohun ìjà ikú sílẹ̀;
14 Ẹni tí ó lóyún ohun búburú,
15 Ẹni tí ó gbẹ́ ọ̀fìn, tí ó kó o jáde
16 Wàhálà tí ó fà padà sórí rẹ̀;
17 Èmi ó fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí òdodo rẹ̀,