Salmos 7

YOR

1 Olúwa Ọlọ́run mi, ààbò mi wà nínú rẹ;

2 kí wọn ó má ba à fa ọkàn mi ya gẹ́gẹ́ bí kìnnìún,

3 Olúwa Ọlọ́run mi, tí èmi bá ṣe èyí

4 bí èmi bá ṣe ibi sí ẹni tí ń wá àlàáfíà pẹ̀lú mi,

5 nígbà náà, jẹ́ kí ọ̀tá mi lé mi kí wọn sì mú mi;

6 Dìde, Olúwa, nínú ìbínú rẹ;

7 Kí ìpéjọ àwọn ènìyàn yíká.

8 Jẹ́ kí Olúwa ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn.

9 Ọlọ́run Olódodo,

10 Ààbò mi ń bẹ lọ́dọ̀ Ọlọ́run,

11 Ọlọ́run ni onídàájọ́ òtítọ́,

12 Bí kò bá yípadà,

13 Ó ti pèsè ohun ìjà ikú sílẹ̀;

14 Ẹni tí ó lóyún ohun búburú,

15 Ẹni tí ó gbẹ́ ọ̀fìn, tí ó kó o jáde

16 Wàhálà tí ó fà padà sórí rẹ̀;

17 Èmi ó fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí òdodo rẹ̀,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado