1 Ṣàánú fún mi, Ọlọ́run, ṣàánú fún mi,
2 Mo kígbe sókè sí Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo jùlọ,
3 Òun yóò ránṣẹ́ láti ọ̀run wá,
4 Mo wà ní àárín àwọn kìnnìún;
5 Kí a yìn ọ́ Ọlọ́run, ju ọ̀run lọ,
6 Wọ́n ti ta àwọ̀n sílẹ̀ fún ẹsẹ̀ mi:
7 Ọkàn mi ti múra Ọlọ́run;
8 Jí, ìwọ ọkàn mi!
9 Èmi ó máa yìn ọ́, Olúwa, láàrín àwọn orílẹ̀-èdè;
10 Nítorí títóbi ní ìfẹ́ rẹ, tí ó dé ọ̀run;
11 Gbígbéga ni ọ́, Ọlọ́run, ju àwọn ọ̀run lọ;