Salmos 56

YOR

1 Ṣàánú fún mi, Ọlọ́run,

2 Àwọn ọ̀tá mi ń lé mi ní gbogbo ọjọ́,

3 Nígbà tí ẹ̀rù bà ń bà mí,

4 Nínú Ọlọ́run èmi yóò máa yìn ọ̀rọ̀ rẹ,

5 Wọn ń yí ọ̀rọ̀ mí ní gbogbo ọjọ́,

6 Wọn kó ara wọn jọ, wọ́n ba.

7 San ẹ̀san iṣẹ́ búburú wọ́n fún wọn;

8 Kọ ẹkún mi sílẹ̀;

9 Nígbà náà ni àwọn ọ̀tá mi yóò pẹ̀yìndà

10 Nínú Ọlọ́run, ẹni tí mo yìn ọ̀rọ̀ rẹ̀

11 nínú Ọlọ́run ni ìgbẹ́kẹ̀lé mi:

12 Mo jẹ́ ẹ̀jẹ́ lábẹ́ rẹ Ọlọ́run:

13 Nítorí ìwọ tí gbà mí lọ́wọ́ ikú

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado