1 Ṣàánú fún mi, Ọlọ́run,
2 Àwọn ọ̀tá mi ń lé mi ní gbogbo ọjọ́,
3 Nígbà tí ẹ̀rù bà ń bà mí,
4 Nínú Ọlọ́run èmi yóò máa yìn ọ̀rọ̀ rẹ,
5 Wọn ń yí ọ̀rọ̀ mí ní gbogbo ọjọ́,
6 Wọn kó ara wọn jọ, wọ́n ba.
7 San ẹ̀san iṣẹ́ búburú wọ́n fún wọn;
8 Kọ ẹkún mi sílẹ̀;
9 Nígbà náà ni àwọn ọ̀tá mi yóò pẹ̀yìndà
10 Nínú Ọlọ́run, ẹni tí mo yìn ọ̀rọ̀ rẹ̀
11 nínú Ọlọ́run ni ìgbẹ́kẹ̀lé mi:
12 Mo jẹ́ ẹ̀jẹ́ lábẹ́ rẹ Ọlọ́run:
13 Nítorí ìwọ tí gbà mí lọ́wọ́ ikú