Salmos 55

YOR

1 Fi etí sí àdúrà mi, Ọlọ́run,

2 gbọ́ mi kí o sì dá mi lóhùn.

3 Sí ohùn àwọn ọ̀tá ni,

4 Ọkàn mi wà nínú ìrora pẹ̀lú;

5 Ìbẹ̀rù àti ìwárìrì wa sí ara mi;

6 Èmi sọ pé, “Èmi ìbá ní ìyẹ́ bí àdàbà!

7 Èmi ìbá sálọ, jìnnà réré,

8 èmi ìbá yára lọ́ si ibùgbé mi ní ibi ààbò,

9 Da àwọn ẹni búburú láàmú, Olúwa, da ahọ́n wọn rú,

10 Ọ̀sán àti òru ni wọ́n fi ń rìn gbogbo odi kiri;

11 Ìwà búburú ń bẹ ní àárín rẹ̀;

12 Tí ọ̀tá bá tàbùkù mi,

13 Ṣùgbọ́n tí ó bá ṣe ìwọ, ọkùnrin bí ẹgbẹ́ mi,

14 pẹ̀lú ẹni tí èmi ti jẹ ìgbádùn adùn ìdàpọ̀,

15 Kí ikú kí ó dé bá wọn,

16 Ṣùgbọ́n èmi pe Ọlọ́run;

17 Ní alẹ́, ní òwúrọ̀ àti ní ọ̀sán

18 Ó rà mí padà láìléwu

19 Ọlọ́run yóò gbọ́, yóò sì pọ́n wọn lójú àní,

20 Ọ̀rẹ́ mi yìí ti dalẹ̀ èmi ọ̀rẹ́ rẹ̀;

21 Ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀ kúnná ju òrí-àmọ́,

22 Gbé ẹrù rẹ lọ sí ọ̀dọ̀ Olúwa

23 Ṣùgbọ́n ìwọ, Ọlọ́run, ni yóò mu àwọn ọ̀tá mi

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado