1 Fi etí sí àdúrà mi, Ọlọ́run,
2 gbọ́ mi kí o sì dá mi lóhùn.
3 Sí ohùn àwọn ọ̀tá ni,
4 Ọkàn mi wà nínú ìrora pẹ̀lú;
5 Ìbẹ̀rù àti ìwárìrì wa sí ara mi;
6 Èmi sọ pé, “Èmi ìbá ní ìyẹ́ bí àdàbà!
7 Èmi ìbá sálọ, jìnnà réré,
8 èmi ìbá yára lọ́ si ibùgbé mi ní ibi ààbò,
9 Da àwọn ẹni búburú láàmú, Olúwa, da ahọ́n wọn rú,
10 Ọ̀sán àti òru ni wọ́n fi ń rìn gbogbo odi kiri;
11 Ìwà búburú ń bẹ ní àárín rẹ̀;
12 Tí ọ̀tá bá tàbùkù mi,
13 Ṣùgbọ́n tí ó bá ṣe ìwọ, ọkùnrin bí ẹgbẹ́ mi,
14 pẹ̀lú ẹni tí èmi ti jẹ ìgbádùn adùn ìdàpọ̀,
15 Kí ikú kí ó dé bá wọn,
16 Ṣùgbọ́n èmi pe Ọlọ́run;
17 Ní alẹ́, ní òwúrọ̀ àti ní ọ̀sán
18 Ó rà mí padà láìléwu
19 Ọlọ́run yóò gbọ́, yóò sì pọ́n wọn lójú àní,
20 Ọ̀rẹ́ mi yìí ti dalẹ̀ èmi ọ̀rẹ́ rẹ̀;
21 Ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀ kúnná ju òrí-àmọ́,
22 Gbé ẹrù rẹ lọ sí ọ̀dọ̀ Olúwa
23 Ṣùgbọ́n ìwọ, Ọlọ́run, ni yóò mu àwọn ọ̀tá mi