1 Gbà mí, Ọlọ́run nípa orúkọ rẹ:
2 Gbọ́ àdúrà mi, Ọlọ́run;
3 Àwọn agbéraga àlejò dìde sí mí.
4 Kíyèsi i Ọlọ́run ni olùrànlọ́wọ́ mi;
5 Jẹ́ kí ibi padà sẹ́yìn sí àwọn tí ń sọ̀rọ̀ ìbàjẹ́ sí mi;
6 Èmí yóò rú ẹbọ àtinúwá sí ọ,
7 Nítorí tí ó yọ mí kúrò nínú ibi gbogbo