1 Ẹ̀yin ha ń sọ òdodo nítòótọ́
2 Bẹ́ẹ̀ kọ́, nínú ọkàn yín ẹ̀yìn ń gbèrò àìṣòdodo,
3 Ní inú ìyá wọn wá ni ènìyàn búburú tí ṣìnà,
4 Oró wọn dàbí oró ejò,
5 tí kò ní gbọ́ ìpè àwọn atunilójú,
6 Ká eyín ẹnu wọn, Ọlọ́run;
7 Jẹ́ kí wọn parẹ́ bí omi tó ń sàn lọ;
8 Jẹ́ kí wọn rí bí ìgbín tí rẹ̀ dànù tí ó sì ṣègbé
9 Kí ìkòkò yín kí ó tó mọ ìgbóná ẹ̀gún;
10 Olódodo yóò yọ̀ nígbà a bá ń gbẹ̀san wọn,
11 Àwọn ènìyàn yóò wí pé,