Salmos 51

YOR

1 Ṣàánú fún mi, Ọlọ́run,

2 Wẹ gbogbo àìṣedéédéé mi nù kúrò

3 Nítorí mo mọ̀ gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ mi,

4 Sí ọ, ìwọ nìkan ṣoṣo, ni mo dẹ́ṣẹ̀ sí

5 Nítòótọ́, nínú ẹ̀ṣẹ̀ ni a ti bí mi,

6 Nítòótọ́ ìwọ fẹ́ òtítọ́ ní inú;

7 Wẹ̀ mí pẹ̀lú ewé hísópù, èmi yóò sì mọ́;

8 Jẹ́ kí n gbọ́ ayọ̀ àti inú dídùn;

9 Pa ojú rẹ̀ mọ́ kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ mi

10 Dá ọkàn mímọ́ sí inú mi, Ọlọ́run,

11 Má ṣe jù mi nù kúrò níwájú rẹ,

12 Mú ayọ̀ ìgbàlà rẹ tọ̀ mí wá,

13 Nígbà náà ni èmi yóò máa kọ́ àwọn olùrékọjá ní ọ̀nà rẹ,

14 Gbà mí kúrò lọ́wọ́ ẹ̀bi ẹ̀jẹ̀, Ọlọ́run,

15 Olúwa, ṣí mi ní ètè mi gbogbo,

16 Nítorí ìwọ kò ní inú dídùn sí ẹbọ, tí èmi kò bá mú wá;

17 Ẹbọ Ọlọ́run ni ìròbìnújẹ́ ọkàn ìròbìnújẹ́ àti ìrora àyà.

18 Ṣe rere ní dídùn inú rẹ sí Sioni,

19 Nígbà náà ni inú rẹ yóò dùn sí ẹbọ òdodo,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado