1 Olúwa, Ọlọ́run alágbára,
2 Láti Sioni wá, pípé ni ẹwà,
3 Ọlọ́run ń bọ̀,
4 Yóò sì pe àwọn ọ̀run láti òkè wá jọ àti ayé,
5 “Kó àwọn ènìyàn mímọ́ jọ fún mi
6 Àwọn ọ̀run yóò sì sọ̀rọ̀ òdodo rẹ̀,
7 “Ẹ gbọ́, ẹ̀yin ènìyàn mi, èmi yóò si sọ̀rọ̀, ìwọ Israẹli, èmi yóò jẹ́rìí sí ọ:
8 Èmi kí yóò bá ọ wí
9 Èmí kò fẹ́ kí ó mú akọ màlúù láti inú ilé tí o kọ́ fún un,
10 nítorí gbogbo ẹran igbó ni tèmi
11 Èmi mọ gbogbo ẹyẹ ní orí àwọn òkè ńlá
12 Bí ebi tilẹ̀ ń pa mí, èmi kì yóò sọ fún ọ,
13 Ǹjẹ́ èmi yóò ha jẹ ẹran akọ màlúù tàbí
14 “Rú ẹbọ ọpẹ́ sí Ọlọ́run,
15 Kí o sì pè mí ní ọjọ́ ìpọ́njú,
16 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run sọ fún àwọn, ènìyàn búburú:
17 Ìwọ kórìíra àṣẹ mi,
18 Nígbà tí ìwọ rí olè, ìwọ dára pọ̀ mọ́ ọn,
19 Ìwọ lo ẹnu rẹ fún aburú,
20 Ní ìgbà gbogbo ìwọ ń sọ̀rọ̀ sí arákùnrin rẹ,
21 Àwọn nǹkan wọ̀nyí ni ìwọ ti ṣe, mo sì dákẹ́;
22 “Ǹjẹ́ ìwọ ro èyí wò, ẹ̀yin tí ó gbàgbé Ọlọ́run.
23 Ẹni tí ó ba ní ẹbọ ọrẹ-ọpẹ́ bu ọlá fún mi; kí ó sì tún ọ̀nà rẹ̀ ṣe,