Salmos 50

YOR

1 Olúwa, Ọlọ́run alágbára,

2 Láti Sioni wá, pípé ni ẹwà,

3 Ọlọ́run ń bọ̀,

4 Yóò sì pe àwọn ọ̀run láti òkè wá jọ àti ayé,

5 “Kó àwọn ènìyàn mímọ́ jọ fún mi

6 Àwọn ọ̀run yóò sì sọ̀rọ̀ òdodo rẹ̀,

7 “Ẹ gbọ́, ẹ̀yin ènìyàn mi, èmi yóò si sọ̀rọ̀, ìwọ Israẹli, èmi yóò jẹ́rìí sí ọ:

8 Èmi kí yóò bá ọ wí

9 Èmí kò fẹ́ kí ó mú akọ màlúù láti inú ilé tí o kọ́ fún un,

10 nítorí gbogbo ẹran igbó ni tèmi

11 Èmi mọ gbogbo ẹyẹ ní orí àwọn òkè ńlá

12 Bí ebi tilẹ̀ ń pa mí, èmi kì yóò sọ fún ọ,

13 Ǹjẹ́ èmi yóò ha jẹ ẹran akọ màlúù tàbí

14 “Rú ẹbọ ọpẹ́ sí Ọlọ́run,

15 Kí o sì pè mí ní ọjọ́ ìpọ́njú,

16 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run sọ fún àwọn, ènìyàn búburú:

17 Ìwọ kórìíra àṣẹ mi,

18 Nígbà tí ìwọ rí olè, ìwọ dára pọ̀ mọ́ ọn,

19 Ìwọ lo ẹnu rẹ fún aburú,

20 Ní ìgbà gbogbo ìwọ ń sọ̀rọ̀ sí arákùnrin rẹ,

21 Àwọn nǹkan wọ̀nyí ni ìwọ ti ṣe, mo sì dákẹ́;

22 “Ǹjẹ́ ìwọ ro èyí wò, ẹ̀yin tí ó gbàgbé Ọlọ́run.

23 Ẹni tí ó ba ní ẹbọ ọrẹ-ọpẹ́ bu ọlá fún mi; kí ó sì tún ọ̀nà rẹ̀ ṣe,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado