1 Èéṣe tí ìwọ fi ń ṣe féfé nínú ìwà ìkà, ìwọ alágbára ọkùnrin?
2 Ahọ́n rẹ̀ ń gbìmọ̀ ìparun;
3 Ìwọ fẹ́ràn ibi ju ìre lọ,
4 Ìwọ fẹ́ràn ọ̀rọ̀ ìpanilára gbogbo,
5 Ọlọ́run yóò sì lù ọ́ bolẹ̀ láéláé,
6 Àwọn olódodo yóò rí, wọn yóò sì bẹ̀rù
7 “Èyí ni ọkùnrin náà ti kò fi Ọlọ́run ṣe agbára rẹ̀,
8 Ṣùgbọ́n èmi dàbí igi Olifi
9 Èmi yóò yìn ọ títí fún ohun tí ó ti ṣe;