Salmos 41

YOR

1 Ìbùkún ni fún ẹni tí ó ń ro ti aláìní:

2 Olúwa yóò dáàbò bò ó yóò sì pa ọkàn rẹ̀ mọ́:

3 Olúwa yóò gbà á lórí àkéte àìsàn rẹ̀

4 Ní ti èmi, mo wí pé “Olúwa, ṣàánú fún mi;

5 Àwọn ọ̀tá mi ń sọ̀rọ̀ mi nínú àrankàn, pé,

6 Nígbàkígbà tí ẹnìkan bá wá wò mí,

7 Àwọn ọ̀tá mi gbìmọ̀ papọ̀ nípa mi;

8 wọ́n wí pé, “Ohun búburú ni ó dì mọ́ ọn ṣinṣin

9 Pàápàá, ọ̀rẹ́ mi tímọ́tímọ́, ẹni tí mo gbẹ́kẹ̀lé,

10 Ṣùgbọ́n ìwọ Olúwa, ṣàánú fún mi;

11 Èmi mọ̀ pé inú rẹ̀ dùn sí mi,

12 Bí ó ṣe tèmi ni

13 Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado