1 Ìbùkún ni fún ẹni tí ó ń ro ti aláìní:
2 Olúwa yóò dáàbò bò ó yóò sì pa ọkàn rẹ̀ mọ́:
3 Olúwa yóò gbà á lórí àkéte àìsàn rẹ̀
4 Ní ti èmi, mo wí pé “Olúwa, ṣàánú fún mi;
5 Àwọn ọ̀tá mi ń sọ̀rọ̀ mi nínú àrankàn, pé,
6 Nígbàkígbà tí ẹnìkan bá wá wò mí,
7 Àwọn ọ̀tá mi gbìmọ̀ papọ̀ nípa mi;
8 wọ́n wí pé, “Ohun búburú ni ó dì mọ́ ọn ṣinṣin
9 Pàápàá, ọ̀rẹ́ mi tímọ́tímọ́, ẹni tí mo gbẹ́kẹ̀lé,
10 Ṣùgbọ́n ìwọ Olúwa, ṣàánú fún mi;
11 Èmi mọ̀ pé inú rẹ̀ dùn sí mi,
12 Bí ó ṣe tèmi ni
13 Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli,