1 Bí àgbọ̀nrín ti ń mí hẹlẹ sí ipa odò omi,
2 Òùngbẹ Ọlọ́run ń gbẹ ọkàn mi, fún Ọlọ́run alààyè.
3 Oúnjẹ mi ni omijé mi
4 Nígbà tí mo bá rántí nǹkan yìí,
5 Èéṣe tí o fi ń rẹ̀wẹ̀sì, ìwọ ọkàn mi?
6 Ọlọ́run mi, ọkàn mi ń rẹ̀wẹ̀sì nínú mi:
7 Ibú omi ń pe ibú omi
8 Ní ọ̀sán ní Olúwa ran ìfẹ́ rẹ̀,
9 Èmi wí fún Ọlọ́run àpáta mi,
10 Bí ẹni pé idà egungun mi ni ẹ̀gàn tí
11 Èéṣe tí ìwọ fi ń rẹ̀wẹ̀sì, ìwọ ọkàn mi?