1 Mo wí pé, “Èmi yóò ṣọ́ ọ̀nà mi
2 Mo fi ìdákẹ́ ya odi;
3 Àyà mi gbóná ní inú mi.
4 “Olúwa, jẹ́ kí èmi kí ó mọ òpin mi,
5 Ìwọ ti ṣe ayé mi
6 “Nítòótọ́ ni olúkúlùkù ń rìn kiri bí òjìji.
7 “Ṣùgbọ́n ní ìsinsin yìí,
8 Gbà mí lọ́wọ́ ìrékọjá mi gbogbo.
9 Mo dákẹ́ jẹ́ẹ́;
10 Mú pàṣán rẹ kúrò ní ara mi;
11 Ìwọ fi ìbáwí kìlọ̀
12 “Gbọ́ àdúrà mi, Olúwa,
13 Dá mi sí, kí èmi lè ní agbára,