Salmos 37

YOR

1 Má ṣe ìkanra nítorí àwọn olùṣe búburú,

2 nítorí pé wọn yóò gbẹ bí i koríko,

3 Gbẹ́kẹ̀lé Olúwa, kí o sì máa ṣe rere;

4 Ṣe inú dídùn sí Olúwa;

5 Fi ọ̀nà rẹ lé Olúwa lọ́wọ́;

6 Yóò sì mú kí òdodo rẹ̀ jáde bí ìmọ́lẹ̀ òwúrọ̀,

7 Ìwọ dákẹ́ jẹ́ẹ́ níwájú Olúwa,

8 Fàsẹ́yìn nínú inúbíbí, kí o sì kọ ìkáàánú sílẹ̀,

9 Nítorí tí á ó gé àwọn olùṣe búburú kúrò,

10 Síbẹ̀ nígbà díẹ̀ sí i, àwọn ènìyàn búburú kì yóò sí mọ̀;

11 Ṣùgbọ́n àwọn ọlọ́kàn tútù ni yóò jogún ilẹ̀ náà,

12 Ènìyàn búburú di rìkíṣí sí olóòtítọ́,

13 ṣùgbọ́n Olúwa rẹ́rìn-ín sí àwọn ènìyàn búburú,

14 Ènìyàn búburú fa idà yọ,

15 Idà wọn yóò wọ àyà wọn lọ,

16 Ohun díẹ̀ tí olódodo ní,

17 nítorí pé a óò ṣẹ́ ọwọ́ àwọn ènìyàn búburú,

18 Olúwa mọ àwọn ọjọ́ àwọn tó dúró ṣinṣin,

19 Ojú kì yóò tì wọ́n ní àkókò ibi,

20 Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn búburú yóò ṣègbé.

21 Àwọn ènìyàn búburú yá, wọn kò sì san án padà,

22 nítorí àwọn tí Olúwa bá bùkún ni yóò jogún ilẹ̀ náà,

23 Ìlànà ìgbésẹ̀ ènìyàn rere wá láti ọ̀dọ̀ Olúwa wá,

24 bí ó tilẹ̀ ṣubú a kì yóò ta á nù pátápátá,

25 Èmi ti wà ni èwe, báyìí èmi sì dàgbà;

26 Aláàánú ni òun nígbà gbogbo a máa yá ni;

27 Lọ kúrò nínú ibi, kí o sì máa ṣe rere;

28 Nítorí pé Olúwa fẹ́ràn ìdájọ́ òtítọ́,

29 Olódodo ni yóò jogún ilẹ̀ náà,

30 Ẹnu olódodo sọ̀rọ̀ ọgbọ́n,

31 Òfin Ọlọ́run rẹ̀ ń bẹ ní àyà wọn;

32 Ènìyàn búburú ń ṣọ́ olódodo,

33 Olúwa kì yóò fi lé e lọ́wọ́ kì yóò sì dá a lẹ́bi,

34 Dúró de Olúwa,

35 Èmi ti rí ènìyàn búburú tí ń hu ìwà ìkà,

36 ṣùgbọ́n ní ìṣẹ́jú kan sí i ó kọjá lọ, sì kíyèsi, kò sì sí mọ́;

37 Máa kíyèsi ẹni pípé, kí o sì wo ẹni tó dúró ṣinṣin;

38 Ṣùgbọ́n àwọn olùrékọjá ni a ó parun papọ̀;

39 Ìgbàlà àwọn onídùúró ṣinṣin wá láti ọ̀dọ̀ Olúwa;

40 Olúwa yóò ràn wọ́n lọ́wọ́ yóò sì gbà wọ́n;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado