Salmos 36

YOR

1 Ìré-òfin-kọjá ènìyàn búburú

2 Nítorí pé wọ́n pọ́n ara wọn ní ojú ara wọn

3 Ọ̀rọ̀ ẹnu wọn ni ẹ̀ṣẹ̀ òhun ẹ̀tàn;

4 Wọ́n gbìmọ̀ ìwà ìkà nígbà tí wọ́n wà lórí ibùsùn wọn:

5 Ìdúró ṣinṣin ìfẹ́ rẹ, ìwọ Olúwa, ó ga dé ọ̀run,

6 Òdodo rẹ dàbí àwọn òkè Ọlọ́run,

7 Báwo ni ìṣeun ìdúró ṣinṣin ìfẹ́ rẹ ti tó! Ọlọ́run!

8 Àsè ilé rẹ yóò tẹ́ wọn lọ́rùn gidigidi;

9 Nítorí pé pẹ̀lú rẹ ni orísun ìyè wà:

10 Mú ìṣeun ìfẹ́ ẹ̀ rẹ sí àwọn tí ó mọ̀ ọ́n

11 Má ṣe jẹ́ kí ẹsẹ̀ agbéraga kí ó wá sí orí mi,

12 Níbẹ̀ ni àwọn oníṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀ gbé ṣubú sí:

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado