1 Ìré-òfin-kọjá ènìyàn búburú
2 Nítorí pé wọ́n pọ́n ara wọn ní ojú ara wọn
3 Ọ̀rọ̀ ẹnu wọn ni ẹ̀ṣẹ̀ òhun ẹ̀tàn;
4 Wọ́n gbìmọ̀ ìwà ìkà nígbà tí wọ́n wà lórí ibùsùn wọn:
5 Ìdúró ṣinṣin ìfẹ́ rẹ, ìwọ Olúwa, ó ga dé ọ̀run,
6 Òdodo rẹ dàbí àwọn òkè Ọlọ́run,
7 Báwo ni ìṣeun ìdúró ṣinṣin ìfẹ́ rẹ ti tó! Ọlọ́run!
8 Àsè ilé rẹ yóò tẹ́ wọn lọ́rùn gidigidi;
9 Nítorí pé pẹ̀lú rẹ ni orísun ìyè wà:
10 Mú ìṣeun ìfẹ́ ẹ̀ rẹ sí àwọn tí ó mọ̀ ọ́n
11 Má ṣe jẹ́ kí ẹsẹ̀ agbéraga kí ó wá sí orí mi,
12 Níbẹ̀ ni àwọn oníṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀ gbé ṣubú sí: