1 Ìbùkún ni fún àwọn
2 Ìbùkún ni fún ọkùnrin náà
3 Nígbà tí mo dákẹ́,
4 Nítorí pé ni ọ̀sán àti ní òru
5 Èmi jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ mi sí ọ
6 Nítorí náà jẹ́ kí gbogbo àwọn olódodo máa gbà àdúrà sí ọ
7 Ìwọ ni ibi ìpamọ́ mi;
8 Èmi yóò kọ́ ọ, èmi yóò sì fi ẹsẹ̀ rẹ lé ọ̀nà tí ìwọ yóò rìn
9 Má ṣe dàbí ẹṣin tàbí ìbáaka,
10 Ọ̀pọ̀ ìkáàánú ní yóò wà fún ènìyàn búburú,
11 Ẹ yọ̀ nínú Olúwa, kí ẹ sì ní inú dídùn, ẹ̀yìn olódodo;