1 Ṣe ìdájọ́ mi, Olúwa,
2 Wádìí mi wò, Ìwọ Olúwa, kí o sì dán mi wò,
3 nítorí ìfẹ́ ẹ̀ rẹ tí ó dúró ṣinṣin ń bẹ níwájú mi,
4 Èmi kò jókòó pẹ̀lú aláìṣòótọ́,
5 Èmi ti kórìíra àwùjọ àwọn ènìyàn búburú
6 Èmí ó wẹ ọwọ́ mi ní àìlẹ́ṣẹ̀,
7 Èmi yóò kọrin sókè àní orin ọpẹ́,
8 Háà Olúwa, èmí ń fẹ́ ilé rẹ níbi tí ìwọ ń gbé,
9 Má ṣe gbá mi dànù pẹ̀lú àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀,
10 àwọn tí ọwọ́ wọn kún fún ìwà ibi,
11 Ṣùgbọ́n èmi ó máa rìn nínú ìwà títọ́;
12 Ẹsẹ̀ mi dúró lórí ilẹ̀ tí ó tẹ́jú;