Salmos 25

YOR

1 Olúwa,

2 Ọlọ́run, èmi gbẹ́kẹ̀lé ọ;

3 Ẹni tí ó dúró tì ọ́

4 Fi ọ̀nà rẹ hàn mí, Olúwa,

5 ṣe amọ̀nà mi nínú òtítọ́ ọ̀ rẹ, kí o sì kọ́ mi,

6 Rántí, Olúwa àánú àti ìfẹ́ ẹ̀ rẹ̀ ńlá,

7 Má ṣe rántí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ ìgbà èwe mi

8 Rere àti ẹni ìdúró ṣinṣin ní Olúwa:

9 Ó ṣe amọ̀nà àwọn onírẹ̀lẹ̀ ni ohun tí ó dára,

10 Gbogbo ipa ọ̀nà Olúwa ni ìfẹ́ àti òdodo tí ó dúró ṣinṣin,

11 Nítorí orúkọ rẹ, Olúwa,

12 Àwọn wo ni ó bẹ̀rù Olúwa?

13 Wọn yóò lo ọjọ́ wọn nínú àlàáfíà,

14 Olúwa fi ọkàn tán, àwọn tí o bẹ̀rù u rẹ̀;

15 Ojú mi gbé sókè sọ́dọ̀ Olúwa,

16 Yípadà sí mi, kí o sì ṣe oore fún mi;

17 Tì mí lẹ́yìn kúrò nínú ìpọ́njú àyà mi;

18 Kíyèsi ìjìyà àti wàhálà mi,

19 Kíyèsi ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ọ̀tá mi,

20 Pa ọkàn mi mọ́, kí o sì gbà mí sílẹ̀;

21 Jẹ́ kí òtítọ́ inú àti ìdúró ṣinṣin kí ó pa mí mọ́;

22 Ra Israẹli padà, Ìwọ Ọlọ́run,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado