1 Olúwa,
2 Ọlọ́run, èmi gbẹ́kẹ̀lé ọ;
3 Ẹni tí ó dúró tì ọ́
4 Fi ọ̀nà rẹ hàn mí, Olúwa,
5 ṣe amọ̀nà mi nínú òtítọ́ ọ̀ rẹ, kí o sì kọ́ mi,
6 Rántí, Olúwa àánú àti ìfẹ́ ẹ̀ rẹ̀ ńlá,
7 Má ṣe rántí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ ìgbà èwe mi
8 Rere àti ẹni ìdúró ṣinṣin ní Olúwa:
9 Ó ṣe amọ̀nà àwọn onírẹ̀lẹ̀ ni ohun tí ó dára,
10 Gbogbo ipa ọ̀nà Olúwa ni ìfẹ́ àti òdodo tí ó dúró ṣinṣin,
11 Nítorí orúkọ rẹ, Olúwa,
12 Àwọn wo ni ó bẹ̀rù Olúwa?
13 Wọn yóò lo ọjọ́ wọn nínú àlàáfíà,
14 Olúwa fi ọkàn tán, àwọn tí o bẹ̀rù u rẹ̀;
15 Ojú mi gbé sókè sọ́dọ̀ Olúwa,
16 Yípadà sí mi, kí o sì ṣe oore fún mi;
17 Tì mí lẹ́yìn kúrò nínú ìpọ́njú àyà mi;
18 Kíyèsi ìjìyà àti wàhálà mi,
19 Kíyèsi ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ọ̀tá mi,
20 Pa ọkàn mi mọ́, kí o sì gbà mí sílẹ̀;
21 Jẹ́ kí òtítọ́ inú àti ìdúró ṣinṣin kí ó pa mí mọ́;
22 Ra Israẹli padà, Ìwọ Ọlọ́run,