1 Olúwa ni ìmọ́lẹ̀ mi àti ìgbàlà mi;
2 Nígbà tí àwọn ènìyàn búburú kọjú ìjà sí mi
3 Bí ọmọ-ogun tilẹ̀ yí mi ká tí wọ́n sì dìde sí mi,
4 Ohun kan ni mo béèrè lọ́dọ̀ Olúwa,
5 Nítorí pé ní ìgbà ìpọ́njú
6 Ní ìsinsin yìí, a ti gbé orí mi sókè
7 Gbọ́ ohùn mi nígbà tí ẹ̀mí bá à ń pè, Olúwa,
8 Ọkàn mi wí pé, “Wá ojú u rẹ̀!”
9 Má ṣe fi ojú rẹ pamọ́ kúrò lọ́dọ̀ mi,
10 Bí ìyá àti baba bá kọ̀ mí sílẹ̀,
11 Kọ́ mi ní ọ̀nà rẹ, Olúwa,
12 Má ṣe fi mí lé ìfẹ́ àwọn ọ̀tá mi lọ́wọ́,
13 Èmi ní ìgbàgbọ́ pé,
14 Dúró de Olúwa;