Salmos 21

YOR

1 Háà! Olúwa, ọba yóò yọ̀ nínú agbára rẹ,

2 Nítorí pé ìwọ ti fi ìfẹ́ ọkàn rẹ̀ fún un,

3 Ìwọ ti fi àwọn ìbùkún oore kò ó ni ọ̀nà

4 Ó béèrè fún ìyè, ìwọ sì fi fún un,

5 Ògo rẹ̀ pọ̀ nípasẹ̀ ìṣẹ́gun tí o fi fún un;

6 Dájúdájú, ìwọ ti fi ìbùkún ayérayé fún un:

7 Ọba ní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú Olúwa;

8 Ọwọ́ rẹ yóò wá gbogbo àwọn ọ̀tá a rẹ rí;

9 Nígbà tí ìwọ bá yọ

10 Ìwọ yóò pa ìrandíran wọn run kúrò lórí ilẹ̀,

11 Bí o tilẹ̀ jẹ́ wí pé wọ́n ro èrò ibi sí ọ

12 Nítorí pé ìwọ yóò mú wọn yí ẹ̀yìn wọn padà

13 Gbígbéga ni ọ́ Olúwa, nínú agbára rẹ;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado