1 Kí Olúwa kí ó gbóhùn rẹ ní ọjọ́ ìpọ́njú;
2 Kí ó rán ìrànlọ́wọ́ sí ọ, láti ibi mímọ́
3 Kí ó sì rántí gbogbo ẹbọ rẹ
4 Kí ó fi fún ọ gẹ́gẹ́ bi ti èrò ọkàn rẹ
5 Àwa yóò hó fún ayọ̀ nígbà tí o bá di aṣẹ́gun
6 Nísinsin yìí, èmi mọ̀ wí pé,
7 Àwọn mìíràn gbẹ́kẹ̀ wọn lé kẹ̀kẹ́, àwọn mìíràn gbẹ́kẹ̀ wọn lé ẹṣin,
8 Wọ́n wólẹ̀, ní eékún, wọ́n sì ṣubú,
9 Olúwa, fi ìṣẹ́gun fún ọba!