1 Àwọn ọ̀run ń sọ nípa ti ògo Ọlọ́run;
2 Wọ́n ń fọhùn ní ọjọ́ dé ọjọ́;
3 Kò sí ohùn tàbí èdè
4 Ohùn wọn jáde lọ sí gbogbo orílẹ̀ ayé,
5 Tí ó dàbí ọkọ ìyàwó tí ó ń jáde ti yàrá rẹ̀ wá,
6 Ìjáde lọ rẹ̀ ni láti òpin ọ̀run wá
7 Pípé ni òfin Olúwa,
8 Ìlànà Olúwa tọ̀nà,
9 Ìbẹ̀rù Olúwa mọ́,
10 Wọn ṣọ̀wọ́n ju wúrà lọ,
11 Nípa wọn ni a ti ṣí ìránṣẹ́ rẹ̀ létí;
12 Ta ni ó lè mọ àṣìṣe rẹ̀?
13 Wẹ ìránṣẹ́ rẹ mọ́ kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ àmọ̀ọ́n-mọ̀-dá;
14 Jẹ́ kí ọ̀rọ̀ ẹnu mi àti àṣàrò ọkàn mi