Salmos 22

YOR

1 Ọlọ́run mi, Ọlọ́run mi, èéṣe tí ìwọ fi kọ̀ mí sílẹ̀?

2 Ọlọ́run mi, ní ọ̀sán gangan ni mo kígbe, ṣùgbọ́n ìwọ kò dá mi ní ohùn:

3 Ṣùgbọ́n síbẹ̀ ẹni mímọ́ ni Ìwọ;

4 Àwọn baba ńlá wa ní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú rẹ;

5 Ìwọ ni wọ́n sun ẹkún sí, wọ́n sì ní ìgbàlà;

6 Ṣùgbọ́n kòkòrò ní mo jẹ́, kì í sì í ṣe ènìyàn;

7 Gbogbo àwọn tí ó rí mí fi mí ṣe ẹlẹ́yà;

8 “Ó gbẹ́kẹ̀ rẹ̀ lé Olúwa;

9 Síbẹ̀ ìwọ ni ó ti mú mi wá láti inú;

10 Ìwọ ni a fi mí lé lọ́wọ́ láti inú ìyá mi wá,

11 Má ṣe jìnnà sí mi,

12 Ọ̀pọ̀ akọ màlúù yí mi ká;

13 Wọ́n ya ẹnu wọn sì mi bí i kìnnìún tí ń dọdẹ kiri,

14 A dà mí jáde gẹ́gẹ́ bí omi,

15 Agbára mí ti gbẹ bí àpáàdì,

16 Àwọn ajá yí mi ká;

17 Mo lè ka gbogbo àwọn egungun mi;

18 Wọ́n pín aṣọ mi láàrín ara wọn

19 Ṣùgbọ́n ìwọ, Olúwa, má ṣe jìnnà sí mi.

20 Gba ọkàn mi sílẹ̀ lọ́wọ́ idà,

21 Gba ọkàn mi sílẹ̀ lọ́wọ́ kìnnìún;

22 Èmi yóò kéde orúkọ rẹ láàrín arákùnrin àti arábìnrin mi;

23 Ẹ̀yin tí ẹ bẹ̀rù Olúwa, ẹ yìn ín!

24 Nítorí pé òun kò ṣátá, bẹ́ẹ̀ ni kò sì kórìíra

25 Láti ọ̀dọ̀ rẹ̀ ni ìyìn mi yóò ti wá nínú àjọ ńlá;

26 tálákà yóò jẹ yóò sì yó;

27 Gbogbo òpin ayé ni yóò rántí

28 nítorí ìjọba ni ti Olúwa.

29 Bẹ́ẹ̀ náà ni gbogbo àwọn olówó ayé wọn yóò ṣe àsè, wọn yóò sì sìn;

30 Irú-ọmọ rẹ̀ yóò sìn ín;

31 Wọn yóò polongo òdodo rẹ̀

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado