Salmos 2

YOR

1 Èéṣe tí àwọn orílẹ̀-èdè fi ń dìtẹ̀,

2 Àwọn ọba ayé péjọpọ̀

3 Wọ́n sọ pé, “Ẹ jẹ́ kí a fa ẹ̀wọ̀n wọn já,

4 Ẹni tí ó gúnwà lórí ìtẹ́ lọ́run rẹ́rìn-ín;

5 Nígbà náà ni yóò bá wọn wí ní ìbínú rẹ̀

6 “Èmi ti fi ọba mi sí ipò

7 Èmi yóò sì kéde ìpinnu Olúwa:

8 Béèrè lọ́wọ́ mi,

9 Ìwọ yóò fi ọ̀pá irin ṣe àkóso wọn

10 Nítorí náà, ẹ̀yin ọba, ẹ jẹ́ ọlọ́gbọ́n;

11 Ẹ sin Olúwa pẹ̀lú ìbẹ̀rù

12 Fi ẹnu ko ọmọ náà ní ẹnu, kí ó má ba à bínú,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado