1 Èéṣe tí àwọn orílẹ̀-èdè fi ń dìtẹ̀,
2 Àwọn ọba ayé péjọpọ̀
3 Wọ́n sọ pé, “Ẹ jẹ́ kí a fa ẹ̀wọ̀n wọn já,
4 Ẹni tí ó gúnwà lórí ìtẹ́ lọ́run rẹ́rìn-ín;
5 Nígbà náà ni yóò bá wọn wí ní ìbínú rẹ̀
6 “Èmi ti fi ọba mi sí ipò
7 Èmi yóò sì kéde ìpinnu Olúwa:
8 Béèrè lọ́wọ́ mi,
9 Ìwọ yóò fi ọ̀pá irin ṣe àkóso wọn
10 Nítorí náà, ẹ̀yin ọba, ẹ jẹ́ ọlọ́gbọ́n;
11 Ẹ sin Olúwa pẹ̀lú ìbẹ̀rù
12 Fi ẹnu ko ọmọ náà ní ẹnu, kí ó má ba à bínú,