1 Ìbùkún ni fún ọkùnrin náà,
2 Ṣùgbọ́n ayọ̀ inú rẹ̀ wà nínú òfin Olúwa
3 Ó dàbí igi tí a gbìn sí etí odò tí ń sàn,
4 Kò le rí bẹ́ẹ̀ fún àwọn ènìyàn búburú!
5 Nítorí náà àwọn ènìyàn búburú kì yóò le è dìde dúró ní ìdájọ́,
6 Nítorí Olúwa ń ṣọ́ ọ̀nà àwọn olódodo,