Salmos 17

YOR

1 Gbọ́, Olúwa, ẹ̀bẹ̀ òtítọ́ mi;

2 Kí ìdáláre mi wá láti ọ̀dọ̀ rẹ;

3 Ìwọ ti dán àyà mi wò,

4 Bí ó ṣe ti iṣẹ́ ènìyàn nípa ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ,

5 Ìrìn mí ti jẹ mọ́ ọ̀nà rẹ;

6 Èmi ké pè ọ́, Ọlọ́run, nítorí tí ìwọ yóò dá mi lóhùn

7 Fi ìṣeun ìyanu ìfẹ́ ńlá rẹ hàn

8 Pa mí mọ́ bí ẹyin ojú rẹ;

9 lọ́wọ́ àwọn ènìyàn búburú tí ń fóròó mi,

10 Wọ́n pa ọkàn aláìláàánú wọn mọ́,

11 Wọ́n sì mú mi mọ́lẹ̀, wọ́n sì yí mi ká,

12 Wọn dàbí i kìnnìún tí ebi ń pa fún ìjẹ,

13 Dìde, Olúwa, dojúkọ wọ́n, rẹ̀ wọ́n sílẹ̀;

14 Olúwa, nípa ọwọ́ rẹ, gbà mí kúrò lọ́wọ́ irú àwọn ènìyàn bẹ́ẹ̀,

15 Ṣùgbọ́n ní tèmi, èmi yóò máa wo ojú rẹ ní òdodo;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado