1 Pa mí mọ́, Ọlọ́run,
2 Mo sọ fún Olúwa, “Ìwọ ni Olúwa mi,
3 Sí àwọn ènìyàn tí ó wà ní ayé,
4 Ìṣòro àwọn wọ̀n-ọn-nì yóò pọ̀ sí i, àní àwọn tí ń tọ ọlọ́run mìíràn lẹ́yìn.
5 Olúwa, ni ìpín ìní mi tí mo yàn àti ago mi,
6 Okùn ààlà ilẹ̀ ti bọ́ sí ọ̀dọ̀ mi ní ibi dídára;
7 Èmi yóò yin Olúwa, ẹni tí ó gbà mí ní ìyànjú;
8 Mo ti gbé Olúwa síwájú mi ní ìgbà gbogbo.
9 Nítorí èyí, ọkàn mi yọ̀, ahọ́n mi pẹ̀lú ń fò fáyọ̀;
10 nítorí ìwọ kò ní fi ọ̀kan sílẹ̀ nínú isà òkú,
11 Ìwọ ti fi ipa ọ̀nà ìyè hàn mí;