Salmos 16

YOR

1 Pa mí mọ́, Ọlọ́run,

2 Mo sọ fún Olúwa, “Ìwọ ni Olúwa mi,

3 Sí àwọn ènìyàn tí ó wà ní ayé,

4 Ìṣòro àwọn wọ̀n-ọn-nì yóò pọ̀ sí i, àní àwọn tí ń tọ ọlọ́run mìíràn lẹ́yìn.

5 Olúwa, ni ìpín ìní mi tí mo yàn àti ago mi,

6 Okùn ààlà ilẹ̀ ti bọ́ sí ọ̀dọ̀ mi ní ibi dídára;

7 Èmi yóò yin Olúwa, ẹni tí ó gbà mí ní ìyànjú;

8 Mo ti gbé Olúwa síwájú mi ní ìgbà gbogbo.

9 Nítorí èyí, ọkàn mi yọ̀, ahọ́n mi pẹ̀lú ń fò fáyọ̀;

10 nítorí ìwọ kò ní fi ọ̀kan sílẹ̀ nínú isà òkú,

11 Ìwọ ti fi ipa ọ̀nà ìyè hàn mí;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado