1 Ìyìn sí Olúwa àpáta mi,
2 Òun ni Ọlọ́run ìfẹ́ mi àti odi alágbára mi,
3 Olúwa, kí ni ènìyàn tí ìwọ fi ń ṣàníyàn fún un,
4 Ènìyàn rí bí èmi;
5 Tẹ ọ̀run rẹ ba, Olúwa, kí o sì sọ̀kalẹ̀;
6 Rán mọ̀nàmọ́ná kí ó sì fọ́n àwọn ọ̀tá ká;
7 Na ọwọ́ rẹ sílẹ̀ láti ibi gíga;
8 Ẹnu ẹni tí ó kún fún èké
9 Èmi yóò kọ orin tuntun sí ọ
10 Òun ni ó fi ìgbàlà fún àwọn ọba,
11 Gbà mí kí o sì yọ mí nínú ewu
12 Kí àwọn ọmọkùnrin wa
13 Àká wa yóò kún
14 àwọn màlúù wa yóò ru ẹrù wúwo
15 Ìbùkún ni fún àwọn ènìyàn náà tí ó wà ní irú ipò bẹ́ẹ̀,