Salmos 145

YOR

1 Èmi yóò gbé ọ ga, Ọlọ́run ọba mi;

2 Ní ojoojúmọ́ èmi yóò yìn ọ́

3 Títóbi ni Olúwa. Òun sì ni ó yẹ láti fi ìyìn fún púpọ̀púpọ̀:

4 Ìran kan yóò máa yin iṣẹ́ rẹ dé ìran mìíràn;

5 Wọn yóò máa sọ ìyìn ọláńlá rẹ tí ó lógo,

6 Wọn yóò sọ iṣẹ́ agbára rẹ tí ó ní ẹ̀rù

7 Wọn yóò ṣe ìrántí ọ̀pọ̀lọpọ̀

8 Olóore-ọ̀fẹ́ ni Olúwa àti aláàánú

9 Olúwa dára sí ẹni gbogbo;

10 Gbogbo ohun tí ìwọ ti dá ni

11 Wọn yóò sọ ògo ìjọba rẹ

12 kí gbogbo ènìyàn le mọ iṣẹ́ agbára rẹ̀

13 Ìjọba rẹ ìjọba ayérayé ni,

14 Olúwa mú gbogbo àwọn tí ó ṣubú ró

15 Ojú gbogbo ènìyàn ń wò ọ́,

16 Ìwọ ṣí ọwọ́ rẹ

17 Olúwa jẹ́ olódodo ní gbogbo ọ̀nà rẹ̀

18 Olúwa wà ní tòsí gbogbo àwọn tí ń ké pè é,

19 Ó mú ìfẹ́ àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ̀ ṣẹ;

20 Olúwa dá gbogbo àwọn tí ó ní ìfẹ́ sẹ sí

21 Ẹnu mi yóò sọ̀rọ̀ ìyìn Olúwa.

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado