1 Olúwa gbọ́ àdúrà mi,
2 Má ṣe mú ìránṣẹ́ rẹ wá sí ìdájọ́,
3 Ọ̀tá ń lépa mi,
4 Nítorí náà ẹ̀mí mi ṣe rẹ̀wẹ̀sì nínú mi;
5 Èmi rántí ọjọ́ tí ó ti pẹ́;
6 Èmi na ọwọ́ mi jáde sí ọ:
7 Dá mi lóhùn kánkán, Olúwa;
8 Mú mi gbọ́ ìṣeun ìfẹ́ rẹ ní òwúrọ̀:
9 Gbà mí kúrò lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá mi, Olúwa,
10 Kọ́ mi láti ṣe ìfẹ́ rẹ,
11 Nítorí orúkọ rẹ, Olúwa, sọ mi di ààyè;
12 Nínú ìfẹ́ rẹ tí kì í kùnà, ké àwọn ọ̀tá mi kúrò,