1 Èmi yóò yìn ọ́ tinútinú mi gbogbo;
2 Èmi ó máa gbàdúrà sí ìhà tẹmpili mímọ́ rẹ̀
3 Ní ọjọ́ tí mo ké pè é ọ́, ìwọ dá mi lóhùn,
4 Gbogbo àwọn ọba ayé yóò yìn ọ́,
5 Nítòótọ́, wọn ó máa kọrin ní ipa ọ̀nà Olúwa;
6 Bí Olúwa tilẹ̀ ga, síbẹ̀ ó júbà àwọn onírẹ̀lẹ̀;
7 Bí èmi tilẹ̀ ń rìn nínú ìpọ́njú ìwọ ni yóò sọ mi di ààyè;
8 Olúwa yóò ṣe ohun tí ń ṣe tèmi láṣepé;